Loading...
Larger font
Smaller font
Copy
Print
Contents

ISE ISIN ONIGBAGBO

 - Contents
  • Results
  • Related
  • Featured
No results found for: "".
  • Weighted Relevancy
  • Content Sequence
  • Relevancy
  • Earliest First
  • Latest First
    Larger font
    Smaller font
    Copy
    Print
    Contents

    Àwọn Ọlọ́rọ̀ Tí Ó Wà Nínú Bíbélì

    Ọkùnrin ará Etopia yẹn jẹ́ ẹni rere tí ó sì jẹ́ alágbàrá láwùjọ. Ọlọ́run mọ̀ wí pé nígbà tí ó bá yípadà, yóò fún àwọn elòmíràn ní ìmọ́lẹ̀ tí ó ti rí gbà, yóò sì lo agbára rẹ̀ láti tan ìhìnrere kalẹ̀. Àwọn angẹ́lì lọ́run dúró láti ṣe àwárí àwọn tí ń wá ìmọ́lẹ̀ wọ́n sì ń fà wọ́n lọ sí ọ̀dọ̀ Olùgbalà. Nípasẹ̀ iṣẹ́ ìránṣẹ́ Ẹ̀mí Mímọ́ ni Olúwa ti máa ń darí àwọn ènìyàn lọ sí ọ̀dọ̀ ẹni tí yóò fi ìmọ́lẹ̀ hàn wọ́n.-The Acts of Apostles, p. 107.IIO 204.3

    Nígbà tí àwọn Júù fẹ́ pa ìjọ run nígbà tí ó ṣẹ̀ẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀ẹ̀rẹ̀, Níkódémù sì jáde wá ó sì dáàbó bòó. Ó lo ipò rẹ̀ làti mú ìgbàgbọ́ àwọn ọmọlẹ̀yìn rẹ̀ dàgbà, ó sì mú kí ìjọ gbèèrú si ní Jérúsálẹ́mú àti ní mímú kí ìhìnrere ó tẹ̀síwájú. Àwọn tó ti ń fi ígbàkan tẹ̀lé e bu ọlá fún un wá bẹ̀rẹ̀ síí ní kẹ́gàn rẹ̀, tí wọ́n sì ń pọ́n-ọn lójú, ó sì di tálákà nínú ohun ayé síbẹ̀ kò dẹ́kun nínú dídáàbò bo ìgbàgbọ́ rẹ.-The Acts of Apostles, p. 105.IIO 205.1

    Larger font
    Smaller font
    Copy
    Print
    Contents